Videos in compliance with YouTube’s Terms of Use and Privacy Policy
Kín ni yóò ṣẹlẹ̀ bí o bá yàwòrán ayédèrú Kóòdù QR
Láìpẹ́ yìí, àjọ Joint Admissions Matriculation Board (JAMB) kéde pé àwọn ti ṣe ìdádúró Ejikeme Mmesoma láti kọ ìdánwò Unified Tertiary Matriculation Examination (UTME) nítorí ìròyìn ṣíṣe àyídà àwọn èsì ...ìdánwò rẹ ọdún 2023.
Mmesoma ti kọ́kọ́ sọ pé òun kò ṣe àyídà èsì ìdánwò òun rárá, ó ṣàlàyé pé ìrújú wáyé lẹ́yìn ìgbà tí òun ya àwòrán kóòdù QR ní ilé ẹ̀rọ-ayárabí-àsá kan. [+] Show More
Mmesoma ti kọ́kọ́ sọ pé òun kò ṣe àyídà èsì ìdánwò òun rárá, ó ṣàlàyé pé ìrújú wáyé lẹ́yìn ìgbà tí òun ya àwòrán kóòdù QR ní ilé ẹ̀rọ-ayárabí-àsá kan. [+] Show More

Kín ni yóò ṣẹlẹ̀ bí o bá yàwòrán ayédèrú Kóòdù QR
Láìpẹ́ yìí, àjọ Joint Admissions Matriculation Board (JAMB) kéde pé ...

Kedu ihe ga - eme ma ị nyochaa koodu QR adịgboroja
N'oge na-adịbeghị anya, Joint Admissions Matriculation Board (JAMB) ...

Ayédèrú ìkéde lórí rírọ́pò àwọn òṣìṣẹ́ Immigration Service fọ́n ká orí ìkànnì ìtàkurọ̀sọ WhatsApp
Ìròyìn kan tí wọ́n ti ní àjọ Civil Defence, Correctional, Fire àti ...

#Yoruba: Òfintótó ọ̀rọ̀ Keyamo lórí Tíkẹ̀ẹ̀tì Ààrẹ àti Igbákejì rẹ̀ àti ìdá ìbò Atiku ní ọdún 2019
Mínísítà fún Iṣẹ́ àti Ìgbaniṣíṣẹ́ ní orílẹ̀-èdè Nigeria tí ó tún jẹ́ ...

#YorubaFactCheck: Báwo ni ọ̀rọ̀ PeterObi lórí bí òsì ṣe gbilẹ̀ tó ní Àríwá Nigeria ṣe jẹ́ òtítọ́ sí?
Olùdíje fún ipò Ààrẹ Nigeria nínú ẹgbẹ́ òṣèlú Labour Party, Peter Obi, ...

Charly Boy ṣe àgbéjáde àwòrán aṣinilọ́nà tí ó jẹ́ ti #Tinubu tí ó ń wo #PeterObi lórí Tẹ
Òṣeré olórin ọmọ orílẹ̀-èdè Nigeria, Charles Chukwuemeka Oputa, tí gbé ...

#YorubaFactCheck: Reno Omokri pa irọ́ nípa ìwà ọ̀daràn ní orílẹ̀-èdè Nigeria
Reno Omokri tí ó jẹ́ olùrànlọ́wọ́ nígbà kan rí fún Ààrẹ àná Goodluck ...

IRỌ́ ni àtẹ̀jíṣẹ́ Twitter Charly Boy pé àjọ INEC kò ní fi èsì ìdìbò ráńṣẹ́ lórí ẹ̀rọ-ayélujára mọ́!
Òṣeré olórin ọmọ orílẹ̀-èdè Nigeria, Charles Oputa, ẹni tí ìnagijẹ rẹ ...

Ǹjẹ́ òótọ́ ni ọ̀rọ̀ Peter Obi nípa owó tí Nigeria rí lórí ọjà títà ṣílẹ̀ òkèèrè lọ́dún 2022
Olùdíje sípò Ààrẹ lábẹ́ àsìá ẹgbẹ́ òṣèlú Labour (LP), Peter Obi, sọ pé ...

Ṣé ọ̀rọ̀ Atiku lórí iye àwọn aṣàmúlò ìtàkùn ìbánidọ́rẹ̀ẹ́ ní Àríwá orílẹ̀-èdè Nigeria jẹ́ òtítọ́?
Olùdíje fún ipò ààrẹ nínú ẹ̀gbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party ...

Àtọọ́dá ni àwòrán Buhari tí ń kéde àtìlẹ́yìn fún Peter Obi
Àwòrán kan tí ó jẹ́ ti Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Muhammadu Buhari tí ó ...

Buhari pa irọ́ nípa àwọn ètò ìdìbò ẹgbẹ́ nínú ọ̀rọ̀ rẹ lọ́jọ́ ayẹyẹ ìjọba Àwàarawa ti ọdún 2022
Nínú ọ̀rọ̀ tí ó bá gbogbo ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà sọ ní ọjọ́ Kejìlá ...
1
of 4